
Gómìnà Èkìtì, Ọ̀gbẹ́ni Bíọ́dún Oyèbánjí ti kí gbogbo Krìstíánì lónílé àtàlejò kú ọdún Àjínde Jésù Krístì Olúwa wa.
Bẹ́ẹ̀ ló képè wọ́n láti wo ìfẹ́ tí Krístì fihàn nípa fífi ẹ̀mí rẹ̀ lélẹ̀ fún ìdáríjì ẹ̀ṣẹ̀ aráyé, káwọn náà pẹ̀lú ní ìfẹ́ sí ọmọnìkéjì wa fún ìdàgbàsókè ìlú àtorílẹ̀ èdè.
- EKITI RAAMP COORDINATOR, ADUNMO, HAILS OYEBANJI’S DEVELOPMENTAL STRIDES
- The Forthcoming Gubernatorial Election: A Foregone Conclusion Anchored on Performance and Popular Mandate
- Oyebanji Pays Another N2b Gratuity to Retirees.
- EKITI HOS, ACCOUNTING OFFICERS EMBARK ON INSPECTION TOUR OF STATE PROJECTS
- Ekiti OTSD 𝐄𝐯𝐚𝐥𝐮𝐚𝐭es 𝐏𝐞𝐫𝐟𝐨𝐫𝐦ances of State MDAs.