
Gómìnà Èkìtì, Ọ̀gbẹ́ni Bíọ́dún Oyèbánjí ti kí gbogbo Krìstíánì lónílé àtàlejò kú ọdún Àjínde Jésù Krístì Olúwa wa.
Bẹ́ẹ̀ ló képè wọ́n láti wo ìfẹ́ tí Krístì fihàn nípa fífi ẹ̀mí rẹ̀ lélẹ̀ fún ìdáríjì ẹ̀ṣẹ̀ aráyé, káwọn náà pẹ̀lú ní ìfẹ́ sí ọmọnìkéjì wa fún ìdàgbàsókè ìlú àtorílẹ̀ èdè.
- VICE PRESIDENT SHETTIMA, APC GOVERNORS, NATIONAL LEADERS, THOUSANDS OF SUPPORTERS TO CONVERGE IN EKITI FOR OYEBANJI’S GRAND FINALE MEGA RALLY
- Ekiti Flags Off Fertilizer Distribution to Boost Food Production
- Ekiti Government Distributes ₦136 Million Relief Materials to Rainstorm Victims
- Ekiti Inaugurates Public Health Emergency Operations Centre Steering Committee to Boost Emergency Preparedness
- Ekiti Guber Polls: APC inaugurates Campaign Council