
Gómìnà Èkìtì, Ọ̀gbẹ́ni Bíọ́dún Oyèbánjí ti kí gbogbo Krìstíánì lónílé àtàlejò kú ọdún Àjínde Jésù Krístì Olúwa wa.
Bẹ́ẹ̀ ló képè wọ́n láti wo ìfẹ́ tí Krístì fihàn nípa fífi ẹ̀mí rẹ̀ lélẹ̀ fún ìdáríjì ẹ̀ṣẹ̀ aráyé, káwọn náà pẹ̀lú ní ìfẹ́ sí ọmọnìkéjì wa fún ìdàgbàsókè ìlú àtorílẹ̀ èdè.
- EKITI GOVT, FIRM PARTNER ON CATTLE RANCH IN IRELE
- Oyebanji Urges Corps Members to Be Agents of Change, Uphold Neutrality Ahead of Ekiti Polls
- Ekiti holds Monthly Environmental Sanitation Exercise on Saturday
- Ekiti Govt Trains Traffic Officers, Stresses Ethical Conduct
- EKIRS seeks collaboration with labour unions to strengthen tax compliance