
Gómìnà Èkìtì, Ọ̀gbẹ́ni Bíọ́dún Oyèbánjí ti kí gbogbo Krìstíánì lónílé àtàlejò kú ọdún Àjínde Jésù Krístì Olúwa wa.
Bẹ́ẹ̀ ló képè wọ́n láti wo ìfẹ́ tí Krístì fihàn nípa fífi ẹ̀mí rẹ̀ lélẹ̀ fún ìdáríjì ẹ̀ṣẹ̀ aráyé, káwọn náà pẹ̀lú ní ìfẹ́ sí ọmọnìkéjì wa fún ìdàgbàsókè ìlú àtorílẹ̀ èdè.
- Obanla Stool: Ekiti Govt Opposes Imposition, Manipulation of Selection Process
- Ekiti Govt. Commiserates with Oore of Otun, Calls on Residents to observe Improved Road Safety practices
- EKSG receives spare parts donation from Dangote Sinotruk to boost waste management
- Erection of road bumps without approval now an offence in Ekiti — Commissioner
- Oyebanji Lauds President Tinubu’s Reforms, receives Leadership Governor of the Year Award