
Gómìnà Èkìtì, Ọ̀gbẹ́ni Bíọ́dún Oyèbánjí ti kí gbogbo Krìstíánì lónílé àtàlejò kú ọdún Àjínde Jésù Krístì Olúwa wa.
Bẹ́ẹ̀ ló képè wọ́n láti wo ìfẹ́ tí Krístì fihàn nípa fífi ẹ̀mí rẹ̀ lélẹ̀ fún ìdáríjì ẹ̀ṣẹ̀ aráyé, káwọn náà pẹ̀lú ní ìfẹ́ sí ọmọnìkéjì wa fún ìdàgbàsókè ìlú àtorílẹ̀ èdè.
- OYEBANJI: WHY WE ARE HONOURING FORMER EKITI GOVERNORS WITH LEGACY PROJECTS
- Ekiti Information Commissioner Pledges Support for Malaria Larval Source Management Programme
- Ekiti Govt Threatens Revocation of Abandoned Estate Allocations, Warns Land Encroachers
- OYEBANJI NAMES NEW GOVERNMENT BUILDINGS AFTER FORMER EKITI GOVERNORS
- EKITI GOVERNMENT CALLS FOR CALM OVER ALLEGATIONS ARISING FROM ENVIRONMENTAL SANITATION ENFORCEMENT