
Gómìnà Èkìtì, Ọ̀gbẹ́ni Bíọ́dún Oyèbánjí ti kí gbogbo Krìstíánì lónílé àtàlejò kú ọdún Àjínde Jésù Krístì Olúwa wa.
Bẹ́ẹ̀ ló képè wọ́n láti wo ìfẹ́ tí Krístì fihàn nípa fífi ẹ̀mí rẹ̀ lélẹ̀ fún ìdáríjì ẹ̀ṣẹ̀ aráyé, káwọn náà pẹ̀lú ní ìfẹ́ sí ọmọnìkéjì wa fún ìdàgbàsókè ìlú àtorílẹ̀ èdè.
- Ekiti Govt. Assures of Continued Partnership with the media, Urges Responsible Broadcasting
- EKSG PROVIDES FREE MEDICAL CARE FOR FREED KIDNAP VICTIMS
- Oyebanji prioritises border management to enhance security, says Ekiti Deputy Governor
- Ekiti Govt Trains Livestock Value Chain Actors on Modern Cooperative Management
- Democratic Governance Cannot Thrive Without Administrative Legality — Oyebanji