
Gómìnà Èkìtì, Ọ̀gbẹ́ni Bíọ́dún Oyèbánjí ti kí gbogbo Krìstíánì lónílé àtàlejò kú ọdún Àjínde Jésù Krístì Olúwa wa.
Bẹ́ẹ̀ ló képè wọ́n láti wo ìfẹ́ tí Krístì fihàn nípa fífi ẹ̀mí rẹ̀ lélẹ̀ fún ìdáríjì ẹ̀ṣẹ̀ aráyé, káwọn náà pẹ̀lú ní ìfẹ́ sí ọmọnìkéjì wa fún ìdàgbàsókè ìlú àtorílẹ̀ èdè.
- Ekiti SUBEB Flags Off 2026 Enrolment Drive, Urges Parents To Enrol Children
- Ekiti Guber Tribunal Slams SDP Over Lack of Diligent Prosecution of Case
- Ongoing Ekiti Assembly Stewardship Programme Reflects Oyebanji’s Commitment to Transparency — Information Commissioner
- Ekiti Bureau of Special Projects Reaffirms Commitment to High-Impact Infrastructure
- Ekiti First Lady Says Govt Will Intensify Fight Against GBV, Demands Tougher Action Against Perpetrators